Jẹ́nẹ́sísì 13:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Èdè àìyedè sì bẹ̀rẹ̀ láàrin àwọn darandaran Ábúrámù àti ti Lọ́tì. Àwọn ará a Kénánì àti àwọn ará Pérísítì sì ń gbé ní ilẹ̀ náà nígbà náà.

Jẹ́nẹ́sísì 13

Jẹ́nẹ́sísì 13:1-9