Jẹ́nẹ́sísì 11:31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Tẹ́rà sì mú ọmọ rẹ̀ Ábúrámù àti Lọ́tì ọmọ Áránì, ọmọ-ọmọ rẹ̀, ó sì mú Sáráì tí i ṣe aya ọmọ rẹ̀. Ábúrámù pẹ̀lú, gbogbo wọn sì jáde kúrò ní Úrì ti Kálídéà láti lọ sí ilẹ̀ Kénánì. Ṣùgbọ́n nígbà tí wọn dé Áránì wọ́n tẹ̀dó síbẹ̀.

Jẹ́nẹ́sísì 11

Jẹ́nẹ́sísì 11:24-32