Ísíkẹ́lì 46:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ọmọ aládé gbọdọ̀ wà ní àárin wọn, kí ó wọlé nígbà tí wọn bá wọlé, kí ó sì jáde nígbà tí wọn bá jáde.

Ísíkẹ́lì 46

Ísíkẹ́lì 46:3-12