Ísíkẹ́lì 30:5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kúṣì àti Pútì, Lídíà àti gbogbo Árábù, Líbíyà àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ ìlérí yóò ṣubú nípa idà papọ̀ pẹ̀lú Éjíbítì.

Ísíkẹ́lì 30

Ísíkẹ́lì 30:1-8