Ísíkẹ́lì 20:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Mo sì sọ fún wọn pé, “Kí ẹ̀ni kọ̀ọ̀kan yín mú àwọn àwòrán ìríra ti ẹ gbé ṣíwájú yín kúrò, kí ẹ sì má bára yín jẹ́ pẹ̀lú àwọn òrìsà Éjíbítì, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”

Ísíkẹ́lì 20

Ísíkẹ́lì 20:1-17