Ìfihàn 22:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Ìbùkún ni fún àwọn ti ń fọ aṣọ wọn, kí wọ́n lè ni àǹfààní láti wá sí ibi igi ìyè náà, àti kí wọ́n lè gbà àwọn ẹnu-bodè wọ inú ìlú náà.

Ìfihàn 22

Ìfihàn 22:7-16