Ìfihàn 20:8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Yóò sì jáde lọ láti máa tan àwọn orílẹ̀-èdè tí ń bẹ ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ayé jẹ, Gógù àti Mágógú, láti gbá wọn jọ sí ogun: àwọn tí iyè wọn dàbí iyanrìn òkun.

Ìfihàn 20

Ìfihàn 20:1-15