Ìṣe Àwọn Àpósítélì 9:2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

ó bèèrè ìwé lọ́wọ́ rẹ̀ sí sínágọ́gù tí ń bẹ ní ìlú Dámásíkù pé, bí òun bá rí ẹnikẹ́ni tí ń bẹ ni Ọ̀nà yìí, ìbaà ṣe ọkùnrin, tàbí obìnrin, kí òun lè mú wọn ní dídè wá sí Jerúsálémù.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 9

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 9:1-9