Ìṣe Àwọn Àpósítélì 3:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà ti Ọlọ́run jí Jésù Ọmọ rẹ̀ dìde, ó kọ́ rán an sí i yín láti bùkún fún un yín, nípa yíyí olúkúlùkù yín padà kúrò nínú ìwà búburú rẹ̀.”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 3

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 3:19-26