Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:43 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n balógun ọ̀rún ń fẹ́ gba Pọ́ọ̀lù là, ó kọ èrò wọn, ó sì pàṣẹ fún àwọn tí ó lè wẹ̀ kí wọn bọ́ sí òkun lọ sì ilẹ̀.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:38-44