Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:34 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà mo bẹ̀ yín, kí ẹ jẹun díẹ̀, nítorí èyí ni fún ìgbàlà yín: nítorí irun kan kí yóò rẹ́ kúrò lórí ẹnìkan yín.”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:31-41