Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Pọ́ọ̀lù wí fún balógun ọ̀rún àti fún àwọn ọmọ-ogun pé, “Bí kò ṣe pé àwọn wọ̀nyí bá dúró nínú ọkọ̀ ẹ̀yin kí yóò lè là!”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:21-33