Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:29 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí wọ́n bẹ̀rù kí wọn má ṣe rọ́ lu orí òkúta, wọ́n sọ ìdákọ̀ro mẹ́rin sílẹ̀ ni ìdí-ọkọ̀, wọ́n ń rétí òjúmọ́.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:23-36