Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí òòrùn àti ìràwọ̀ kò si hàn lọ́jọ́ púpọ̀, tí ìjì náà kò sì mọ níwọ̀n fún wa, àbá àti là kò sí fún wa mọ́.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 27:18-25