Ìṣe Àwọn Àpósítélì 19:28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n kún fún ìbínú, wọ́n kígbe, wí pé, “Òrìṣà ńlá ni Dáyánà ti ará Éfésù!”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 19

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 19:19-34