Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

A sì yí nínú wọn lọ́kàn padà, wọ́n sì darapọ̀ mọ́ Pọ́ọ̀lù àti Sílà: bákan náà ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn obìnrin ọlọ́lá, kì í se díẹ̀.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17:1-7