Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17:30 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Pẹ̀lúpẹ̀lù ìgbà àìmọ̀ yìí ni Ọlọ́run tí gbójú fò dá; ṣùgbọ́n nísìnyìí ó pàṣẹ fún gbogbo ènìyàn níbi gbogbo láti ronúpìwàdà;

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 17:27-31