Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bí àwa tí nlọ ṣí ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan tí o ní ẹ̀mí ìwosẹ́, pàdé wa, ẹni tí ó fi àfọ̀ṣẹ mú èrè púpọ̀ wá fún àwọn ọ̀gá rẹ̀:

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16:15-22