Ìṣe Àwọn Àpósítélì 12:1 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ní àkókò ìgbà náà ni Hérọ́dù ọba sì nawọ́ rẹ̀ mú àwọn kan lójú nínú ìjọ, pẹ̀lú èrò láti pọ́n wọn lójú.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 12

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 12:1-5