Hósíà 9:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Éfúráímù ti rẹ̀ dànùGbogbo rẹ̀ sì ti rọ,kò sì so èso,Bí wọ́n tilẹ̀ bímọ.Èmi ó pa àwọn ọmọ wọn tí wọ́n fẹ́ràn jùlọ.”

Hósíà 9

Hósíà 9:9-17