10. Nígbà tó bá tẹ́ mi lọ́rùn, èmi yóò fi ìyà jẹ wọ́n;Orílẹ̀ èdè yóò kó ra wọn jọ wọ́n ó sì dojú kọ wọnLáti fi wọn sínú ìdè nítorí ìlọ́po ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
11. Éfúráímù jẹ́ ọmọ màlúù tí atí kọ́, to si fẹ́ràn láti máa pa ọkàlórí ọrun rẹ̀ tó lẹ́wà nièmi ó dí ẹru wúwo léÈmi yóò mú kí a gun Éfúráímù bí ẹṣinJúdà yóò tú ilẹ̀,Jákọ́bù yóò sì fọ́ ogúlùtu rẹ̀
12. Ẹ gbin òdòdó fún ara yínkí ẹ sì ká èso ìfẹ́ àìlópin,Ẹ tu ilẹ̀ yín tí a kòronítorí pé ó ti tó àsìkò láti wá Olúwa,títí tí yóò fi dé,tí yóò sì rọ òjò òdodo lé yín lórí.
13. Ṣùgbọ́n ẹ tí gbìn buburú ẹ si ka ibi,Ẹ ti jẹ èso èkénítorí ẹ tí gbẹ́kẹ̀ lé agbára yínàti àwọn ọ̀pọ̀ jagun jagun yín