Ékísódù 30:21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

wọn yóò sì wẹ ọwọ́ wọn àti ẹsẹ̀ wọn, nítorí kí wọn máa ba à kú. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún Árónì àti irú àwọn ọmọ rẹ̀ fún ìrandìran wọn.”

Ékísódù 30

Ékísódù 30:15-24