Ékísódù 16:1 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìjọ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì mú ọ̀nà wọn pọ̀n kúrò ni Élímù, wọ́n dé sí ijù Sínì tí ó wà láàrin Élímù àti Ṣínáì, ni ọjọ́ kẹẹ̀dógún oṣù kejì tí wọ́n jáde kúrò ni ilẹ̀ Éjíbítì.

Ékísódù 16

Ékísódù 16:1-7