Ékísódù 11:3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

(Olúwa jẹ́ kí wọn rí ojú rere àwọn ará Éjíbítì, pàápàá, Mósè fún ra rẹ̀ di ènìyàn pàtàkì ní ilẹ̀ Éjíbítì ní iwájú àwọn ìjòyè Fáráò àti ní iwájú àwọn ènìyàn pẹ̀lú).

Ékísódù 11

Ékísódù 11:1-10