Dáníẹ́lì 8:22 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìwo mẹ́rin ti ó dípo ọ̀kan tí ó kán dúró, èyí dúró gẹ́gẹ́ bí ìjọba mẹ́rin tí ó dìde láti orílẹ̀ èdè e rẹ̀ ṣùgbọ́n wọn kò ní ní irú agbára kan náà.

Dáníẹ́lì 8

Dáníẹ́lì 8:18-26