Dáníẹ́lì 6:24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ọba pàṣẹ pé, kí a mú àwọn alátakò Dáníẹ́lì wá, kí a jù wọ́n sí inú ihò kìnnìún, pẹ̀lú ìyàwó àti àwọn ọmọ wọn. Kí wọn tó dé ìsàlẹ̀ ihò, kìnnìún lágbára lórí i wọn, wọ́n sì fọ́ gbogbo egungun wọn.

Dáníẹ́lì 6

Dáníẹ́lì 6:17-28