Àwọn Hébérù 9:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bí bẹ́ẹ̀ bá ni oun ìbá tí máa jìyà nígbàkúgbà láti ìpìlẹ̀ ayé: Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ni ó fi ara hàn lẹ́ẹ́kanṣoṣo lópìn ayé láti mi ẹ̀ṣẹ̀ kúrò nípa ẹbọ ara rẹ̀.

Àwọn Hébérù 9

Àwọn Hébérù 9:23-28