Àwọn Hébérù 13:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà ni àwa ṣe ń fi ìgboyà wí pé,“Olúwa ni oluranlọ́wọ́ mi, èmi kì yóò bẹ̀rù;kínni ènìyàn lè ṣe sí mi?”

Àwọn Hébérù 13

Àwọn Hébérù 13:5-12