Àwọn Hébérù 10:37-39 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

37. Nítorí ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ sí i,“Ẹni náà ti ń bọ̀ yóò dé, kí yóò sì jáfara.

38. Ṣùgbọ́n olódodo ni yóò yè nípa ìgbàgbọ́:Ṣùgbọ́n bí o ba fà sẹ́yìn,ọkàn mi kò ní inú dídùn sí i.”

39. Ṣùgbọ́n àwa kò sí nínú àwọn tí ń fà sẹ́yìn sínú ègbé; bí kò ṣe nínú àwọn tí o gbàgbọ́ sí ìgbàlà ọkàn.

Àwọn Hébérù 10