Àwọn Hébérù 10:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àti olukulùkù àlùfáà sì ń dúró lójoojúmọ́ láti ṣiṣẹ́ ìsìn, ó sì ń ṣe ẹbọ kan náà nígbàkúgbà, tí kò lè mú ẹ̀ṣẹ̀ kúrò láé:

Àwọn Hébérù 10

Àwọn Hébérù 10:7-15