Àìsáyà 48:21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Òrùngbẹ kò gbẹ wọ́n nígbà tí ó kó wọnkọjá nínú ihà;ó jẹ́ kí omi ó sàn fún wọn láti inú àpáta;ó fọ́ àpátaomi sì tú jáde.

Àìsáyà 48

Àìsáyà 48:19-22