Àìsáyà 40:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Wò ó, Olúwa àwọn ọmọ-ogun náà ń bọ̀ wá pẹ̀lú agbára,apá rẹ̀ sì ń jọba fún un.Wò ó, ère rẹ̀ sì wà pẹ̀lúu rẹ̀,àti ìdápadà rẹ̀ tí ń bá a bọ̀ wá.

Àìsáyà 40

Àìsáyà 40:1-19