Àìsáyà 28:9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Ta ni ẹni náà tí ó ń gbìyànjú àti kọ́?Ta ni ó sì ń ṣàlàyé ìhìn in rẹ̀ fún?Sí àwọn ọmọdé tí a já lẹ́nu ọmú un wọn,sí àwọn tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà lẹ́nu ọmú.

Àìsáyà 28

Àìsáyà 28:1-11