Àìsáyà 28:18 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Májẹ̀muu yín tí ẹ bá ikú dá ni a ó fagi lé;àdéhùn yín pẹ̀lú ibojì ni kì yóò dúró.Nígbà tí ìbínú gbígbóná náà bá fẹ́ kọjá,a ó ti ipa rẹ̀ lù yín bolẹ̀.

Àìsáyà 28

Àìsáyà 28:10-21