2 Tímótíù 2:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nǹkan wọ̀nyí ni ki ó máa rán wọn létí. Máa kìlọ̀ò fún wọn níwajú Olúwa pé, ki wọn ó yẹra kúrò nínú jíjiyàn ọ̀rọ̀ tí kò léèrè, bí kò ṣe ìparun fún àwọn tí ń gbọ́.

2 Tímótíù 2

2 Tímótíù 2:4-20