2 Ọba 5:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìwé tí ó mú lọ sọ́dọ̀ ọba Ísírẹ́lì kà pé: “Pẹ̀lú ìwé yìí èmi ń rán ìránṣẹ́ mi Námánì sí ọ pé o lè wò ó sàn kúrò nínú ẹ̀tẹ̀ rẹ̀.”

2 Ọba 5

2 Ọba 5:1-10