2 Ọba 4:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Kí ni a lè ṣe fún obìnrin yìí?” Èlíṣà béèrè.Géhásì wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, kò ní ọmọ, ọkọ rẹ̀ náà sì tún di arúgbó.”

2 Ọba 4

2 Ọba 4:6-16