2 Ọba 25:9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

ó sì finá sí ilé Olúwa, ilé ọba àti gbogbo àwọn tí ó wà ní Jérúsálẹ́mù àti gbogbo ilé pàtàkì, ó jó wọn níná.

2 Ọba 25

2 Ọba 25:8-15