2 Ọba 10:3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

yan èyí tí ó dára àti èyí tí ó níye jùlọ nínú àwọn ọmọkùnrin ọ̀gá à rẹ, kí o sì gbé e lé orí ilé baba a rẹ̀. Nígbà náà, kí o sì jà fún, ilé ọ̀gá à rẹ.”

2 Ọba 10

2 Ọba 10:1-10