2 Ọba 10:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Jéhù wí pé, “Wá pẹ̀lú ù mi; kí o sì rí ìtara mi fún Olúwa.” Nígbà náà ó jẹ́ kí ó gun kẹ̀kẹ́ rẹ̀.

2 Ọba 10

2 Ọba 10:8-24