2 Kíróníkà 32:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ó yan àwọn ìjòyè ológun sórí àwọn ènìyàn, ó sì pèwọ́n jọ, níwájú rẹ̀ ní ìbámu ní ìlú ńlá ti Dáfídì. Ó sì ki wọ́n láyà pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí:

2 Kíróníkà 32

2 Kíróníkà 32:1-15