2 Kíróníkà 2:15 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Nísinsin yìí, jẹ́ kí Olúwa mi rán àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ní àlìkámọ̀ àti bálì àti òróró Ólífì náà àti ọtí tí ó ti ṣe ìlérí.

2 Kíróníkà 2

2 Kíróníkà 2:9-18