2 Kíróníkà 18:27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Míkáyà sì wí pe, “Tí ìwọ bá padà ní àlàáfíà, Olúwa kò sọ̀rọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.” Nígbà náà, ó sì fi kún-un pé, “Ẹgbọ́ ọ̀rọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn!”

2 Kíróníkà 18

2 Kíróníkà 18:18-34