1 Sámúẹ́lì 17:55 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bí Ṣọ́ọ̀lù sì ti wo Dáfídì bí ó ṣe ń jáde lọ pàdé Fílístínì, ó wí fún Ábínérì, olórí àwọn ológun rẹ̀ pé, “Ábínérì, ọmọ ta ni ọmọdékùnrin yìí?”Ábínérì dáhùn pe, “Bí ọkàn rẹ̀ ti ń bẹ ní ààyè, ọba èmi kò mọ̀.”

1 Sámúẹ́lì 17

1 Sámúẹ́lì 17:52-58