1 Sámúẹ́lì 15:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Èmi káànú gidigidi pé mo fi Ṣọ́ọ̀lù jọba, nítorí pé ó ti yípadà kúrò lẹ́yìn mi, kò sì pa ọ̀rọ̀ mi mọ́.” Inú Sámúẹ́lì sì bàjẹ́ gidigidi, ó sì képe Olúwa ní gbogbo òru náà.

1 Sámúẹ́lì 15

1 Sámúẹ́lì 15:10-15