1 Sámúẹ́lì 13:12 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

mo rò pé, ‘Àwọn Fílístínì yóò sọ̀kalẹ̀ tọ̀ mí wá ní Gílígálì nísinsìn yìí, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò ì tí ì wá ojúrere Olúwa.’ Báyìí ni mo mú ara mi ní ipa láti rú ẹbọ sísun náà.”

1 Sámúẹ́lì 13

1 Sámúẹ́lì 13:11-15