1 Ọba 7:24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ní ìṣàlẹ̀ etí rẹ̀, kókó wà yíi ká, mẹ́wàá nínú ìgbọ̀nwọ́ kan. Ó yí agbádá náà káàkiri, a dá kókó náà ní ọ̀wọ́ méjì, nígbà tí a dá a.

1 Ọba 7

1 Ọba 7:19-32