1 Ọba 22:48 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Jèhósáfátì kan ọkọ̀ Táríṣíṣì láti lọ sí Ófírì fún wúrà, ṣùgbọ́n wọn kò lọ: nítorí àwọn ọkọ̀ náà fọ́ ní Ésíónì-Gébérì.

1 Ọba 22

1 Ọba 22:42-51