1 Ọba 22:25 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Míkáyà sì wí pé, “Ìwọ yóò rí i ní ọjọ́ náà, nígbà tí ìwọ yóò lọ láti inú ìyẹ̀wù dé ìyẹ̀wù láti fi ara rẹ pamọ́.”

1 Ọba 22

1 Ọba 22:19-29