1 Ọba 21:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ó sì ṣe ohun ìríra gidigidi ní títọ òrìṣà lẹ́yìn, gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí àwọn ará Ámórì ti ṣe, tí Olúwa lé jáde níwájú àwọn ọmọ Ísírẹ́lì.)

1 Ọba 21

1 Ọba 21:20-29